Surah Az-Zalzalah in Yoruba

    الزلزلة

    Surah Az-Zalzalah in Yoruba

    Read Surah Az-Zalzalah in Yoruba (الزلزلة) with Arabic text, Yoruba translation, and audio recitation. Chapter 99 of the Holy Quran, 8 verses — free online.

    Quran in Yoruba · all 114 Surahs

    1

    إِذَا زُلۡزِلَتِ ٱلۡأَرۡضُ زِلۡزَالَهَا

    Nígbà tí wọ́n bá mi ilẹ̀ tìtì ní ìmìtìtì rẹ̀,

    2

    وَأَخۡرَجَتِ ٱلۡأَرۡضُ أَثۡقَالَهَا

    àti (nígbà) tí ilẹ̀ bá tú àwọn ẹrù tó wúwo nínú rẹ̀ jáde,

    3

    وَقَالَ ٱلۡإِنسَٰنُ مَا لَهَا

    ènìyàn yó sì wí pé: “Kí l’ó mú un?”

    4

    يَوۡمَئِذٖ تُحَدِّثُ أَخۡبَارَهَا

    Ní ọjọ́ yẹn ni (ilẹ̀) yóò sọ̀rọ̀ nípa àwọn ìró rẹ̀ (tí ẹ̀dá gbé orí ilẹ̀ ṣe).

    5

    بِأَنَّ رَبَّكَ أَوۡحَىٰ لَهَا

    Nítorí pé dájúdájú Olúwa rẹ l’Ó fún un ní àṣẹ (láti sọ̀rọ̀).

    6

    يَوۡمَئِذٖ يَصۡدُرُ ٱلنَّاسُ أَشۡتَاتٗا لِّيُرَوۡاْ أَعۡمَٰلَهُمۡ

    Ní ọjọ́ yẹn, àwọn ènìyàn yóò máa gba ọ̀nà ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lọ nítorí kí wọ́n lè fi àwọn iṣẹ́ wọn hàn wọ́n.

    7

    فَمَن يَعۡمَلۡ مِثۡقَالَ ذَرَّةٍ خَيۡرٗا يَرَهُۥ

    Nítorí náà, ẹni tí ó bá ṣe iṣẹ́ rere ní òdíwọ̀n ọmọ iná-igún, ó máa rí i.

    8

    وَمَن يَعۡمَلۡ مِثۡقَالَ ذَرَّةٖ شَرّٗا يَرَهُۥ

    Ẹni tí ó bá sì ṣe iṣẹ́ aburú ní òdíwọ̀n ọmọ iná-igún, ó máa rí i.[1]

    [1] Ẹ wo ìtọsẹ̀-ọ̀rọ̀ sūrah al-Wāƙi‘ah; 56:7.

    Az-Zalzalah

    Play